BBC News, Yorùbá - Ìròyìn
Ìròyìn tó ṣe kókó
Makinde sọ̀rọ̀ lórí ibi táwọn agbébọn kó àwọn akẹ́kọ̀ọ́ àti olùkọ́ tí wọ́n jí gbé l'Ogbomoso pamọ́ sí
Gomina ipinlẹ Oyo sọ ninu atẹjade kan to fi sita fawọn akọroyin pe ninu igbo ijọba Old Oyo National Park lawọn ajinigbe naa wa pẹlu awọn akẹkọọ atawọn olukọ ti wọn ji gbe ni ijọba ibilẹ Oriire l'Ogbomoso.
Ọ̀gágun fẹ̀yìntì Rabe Abubakar táwọn agbébọn jí gbé pẹ̀lú ìyàwó rẹ̀ ti kú sí àkàtà àwọn jàndùkú ajínigbé
Adari eto iroyin fun ileeṣẹ ologun Naijiria, Maj Gen Samaila Uba, lo fi idi ọrọ yii mulẹ ninu atẹjade ti o fi sita lonii ọjọ Abamẹta ọjọ kẹtala oṣu Kẹfa yii.
Wo àwọn ohun tó yẹ kí o mọ̀ nípa Kola Oyewo, àgbà òṣèré tíátà Yoruba tó jáde láyé
Àwọn gbajúmọ̀ òṣèré bíi Kunle Afod ati Yomi Ọlọrunlaiye ni wọ́n ti ń daro ipapoda àgbà òṣèré náà.
Ọ̀pọ̀lọpọ̀ wa ló ti rẹ̀ sára àmọ́ inú wa dùn pé a gbòmìnira – Àwọn tó gba ìtúsílẹ̀ lọ́wọ́ Boko Haram
Ọpọ obinrin ati awọn ọmọde ni wọn pe awọn ti wọn ni Boko Haram tu silẹ naa.
Ọdún mẹ́sàn án rèé tí mo ti ń gbé pẹ̀lú àrun kògbóògùn, HIV kìí ṣe ìdájọ́ ikú – Chika Wonder
Ọrọ ti Chika Ekezie ti ọpọ mọ si Chika Wonder sọ ree lasiko to ba BBC sọrọ lori irinajo rẹ pẹlu arun naa.
Fídíò, Mo máa pèsè ètò ẹ̀kọ́ ọ̀fẹ́ fáráàlú tí mo bá di gómìnà ìpínlẹ̀ Ekiti – Segun Akande, Duration 3,53
Segun Akande lo sọ bẹẹ ninu ifọrọwerọ pẹlu BBC Yoruba.
Iléeṣẹ́ ológun Naijiria kéde àwọn agbéṣùmọ̀mí méjì tó juwọ́ sílẹ̀ fún ìjọba
Ileeṣẹ Ologun to fi iroyin naa lede lori ayelujara kede orukọ awọn agbeṣumọmi ti wọn juwọ lẹ naa bii Ismail Mohammed ati Abu Umar.
Ìfẹ̀hónúhàn wáyé káàkiri àwọn ìpínlẹ̀ lórí ààbò tó mẹ́hẹ, bèèrè fífi òpin sí ìjínigbé
Latari bi nnkan ko ṣe fararọ kaakiri lorilẹede Naijiria bayii, paapaa lẹka aabo ati ọrọ aje, ọpọ araalu ni inu wọn ko dun.
Bí ilé aṣojú-ṣòfin ṣe fòńtẹ̀ lu àbá ìdásílẹ̀ ọlọ́pàá ìpínlẹ̀, wo ìlànà ìṣẹ́ wọn, àǹfààní àti ewu rẹ̀
Lasiko ti wọn dibo lori aba naa lati gba a wọle, aṣofin 288 lo faramọ ọn, nigba ti awọn mẹrin sọ pe awọn ko fẹ idasilẹ ọlọpaa ipinlẹ.
Orin, Kò ṣe é má gbọ̀ ọ́, Duration 1,04
Kò ṣeé má gbọ̀ọ́
Kókó ọ̀rọ̀ méje tí Tinubu sọ láti sàmì àyájọ́ June 12 àti àwọn tó gba àmì ẹ̀yẹ fọ́dún kẹtàdínlọ́gbọ̀n ìjọba àwaarawa
Nigba to n ṣide ọrọ rẹ, Aarẹ Tinubu sọ pe bo tilẹ jẹ pe ijọba awaarawa asiko yii ko gun rege, sibẹ, oun lo pẹ ju, tẹni si ni tẹni.
Yàtọ̀ sí June 12, àlàyé rèé nípa àwọn ìṣẹ̀lẹ̀ mẹ́fà míì tí kò bá ti sọ Nàíjíríà sójú ogun abẹ́lé
BBC News Yoruba fi wọ inu itan lọ lati se agbeyẹwo igba meje ọtọọtọ ti ẹpọn agbo Naijiria ti mi, amọ ti Ọlọrun ko jẹ ko ja.
BBC News Yorùbá ti wà lórí ìkànnì WhatsApp
Má jẹ́ kí etí rẹ ó di sí gbogbo ìròyìn ohun tó ń lọ ní Naijiria àti káàkiri àgbáyé. Mọ̀ nípa wọn lórí ìkànnì Whatsapp rẹ
Ìròyìn Àkàgbádùn
Fídíò, Ìdí mẹ́rin tí nǹkan ọkùnrin ṣe máa ń nàró ní àárọ̀ tí wọn bá jí, Duration 1,13
Nínú Fídíò yìí, BBC News Yorùbá ṣe ìwádìí nípa ídí tí nǹkan ọkùnrin ṣe máa ń nàró ní àárọ̀ tí wọn bá jí àti ohun tó ń fà á.
Àwọn agbébọn ṣíná ìbọn bolẹ̀ nígboro South Africa, èèyàn méjìlá kú, mẹ́sàn-án farapa
Gẹgẹ bi akọsilẹ ṣe fi han, orilẹede South Africa wa lara awọn ilu ti wọn ti n pa eeyan ju lagbaaye.
Ẹgbẹ́ City Boys tó ń ṣàtìlẹyìn fún Tinubu l‘Oyo ṣàbẹ̀wó sí Esinele, gbé ohun èlò ìwòsàn kalẹ̀, àmọ́ ẹbí Tíṣà tí agbébọn pa kọ àpò ìrẹsì àti owó Ìyálọ́jà, tíí ṣe ọmọ ààrẹ
Nigba to n sọrọ lasiko abẹwo ọhun, Onireti fi ireti han pe wọn maa ṣawari awọn akẹkọọ atawọn olukọ tawọn ajinigbe naa ji gbe laipẹ, bi o ṣe ni pe ijọba n sapa wọn lati gba itusilẹ awọn eeyan naa.
DSS lọgun pé àgbébọn fẹ́ kọlu iléẹ̀kọ́ l‘Edo, ìjọba ti iléẹ̀kọ́ mẹ́ta pa
Iwe kan lo lu sita lori ayelujara lojiji, eyi ti ikọ alaabo DSS fi sin ileeṣẹ NSCDC ti a mọ si aabo ara ẹni ni aabo ilu ni gberẹ ipakọ, pe awọn afurasi n mura lati kọlu awọn ile ẹkọ l'Edo.
Janmole sọ fún mi kó tó kú nípa ohun tó fẹ́ ṣe pẹ̀lú àbíkẹ́hìn rẹ̀ láìmọ̀ pé ikú ti súnmọ́ - Alfa
BBC News Yorùbá wà níbi àdúrà ọjọ́ kẹjọ gbajúmọ̀ àgbà òṣèré tíátà, olóògbé Fatai Okiki Adeshina Oshin, ti ọpọ eeyan mọ si Janmọlẹ, ohun tí a mú bọ̀ rèé.
Ẹ̀sùn jìbìtì N69m mí-ìn tún wọlé tọ Blessing CEO, yàtọ̀ sí ti 36m tí wọ́n kọ́kọ́ torí rẹ̀ fi pamọ́ sí àhámọ́
Ọjọ Iṣẹgun, ọjọ kẹsan-an oṣu Kẹfa ni ile ẹjọ giga ipinlẹ Eko fi aaye oniduuro silẹ fun Blessing to ti wa lahamọ EFCC lati oṣu to kọja, pẹlu miliọnu mẹwaa naira, ṣugbọn ahamọ EFCC lo pada si.
Kí ni òfin sọ nípa wíwo ilé táwọn ajínigbé bá fi ṣe ibùgbé?
BBC News Yoruba kan si amofin Ademola Owolabi lati ṣalaye ohun ti ofin sọ nipa wiwo ile tawọn ajinigbe ba n lo fi ṣe ibugbe.
MURIC, ẹgbẹ́ Mùsùlùmí nàká àìtọ́ síjọba Oyo pé ó ló ìjínigbé Ogbomoso tako Islam, ìjọba sọ ìdí tí kò ṣe ní fèsì sí ẹ̀sùn náà
Kọmiṣọna fun eto iroyin ni ipinlẹ Oyo, Ọmọba Dotun Oyelade, sọ fun BBC Yoruba wi pe lati ọjọ ti wọn ti ji awọn akẹkọọ ati olukọ lọ ni Esinele ati Yawota l’Ogbomoso ni ijọba ti pinnu pe oun ko ni maa ṣe arohunbọhun pẹlu ẹnikankan lori iṣẹlẹ naa.
Amẹ́ríkà àti Iran ń da àdó olóró bo ara wọn léraléra fún ọjọ́ méjì
Aarẹ Amẹrika, Donald Trump ti fẹsun kan Iran pe o yin ado oloro ba ọkọ ofurufu hẹlikọpita oun ni ẹgbẹ Strait of Hormuz, to si ṣe ikọlu si Iran pada lati gbẹsan.
Rélùwéè yà kúrò lójú irin, èèyàn mẹ́ta kú
Ileeṣẹ NRC to n ri si ọrọ ọkọ ofurufu ni Naijiria, ṣalaye pe ẹka mẹrin lo ya kuro lara ọkọ oju irin naa.
Èèyàn mẹ́rin míràn ni ajínigbé tún pa ní Mowe, kì í ṣe ṣọ́jà nìkan - Iléeṣẹ́ ológun
Ninu atẹjade ti Ọgagun Idereghi Samuel Akari, Igbakeji ọga to n ri si ikede nileeṣẹ ologun 35 Artillery Brigade, Alamala niluu Abeokuta, fi sita lo ti ṣalaye eyi.
Àṣírí abilékọ̀ tó jí ara rẹ̀ gbé, béèrè ₦50m owó ìtúsílẹ̀ tú, ọwọ́ ọlọ́pàá tẹ̀ ẹ́ pẹ̀lú ọ̀rẹ́kùnrin rẹ̀ nílé ìtura
Agbẹnusọ ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Edo, Eno Ikoedem, ni lọjọ kinni oṣu Kẹfa yii ni ọkunrin kan niluu Benin fi to ọlọpaa pe wọn ti ji iyawo oun, Oluchi Ugbowan ẹni ọdun marundinlaadọta gbe lọ.
Ìròyìn Pàtàkì
Kọ́milẹ́kọ̀ọ́
Ẹ tẹ̀lé wa lórí ìkànnì ayélujára
Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn
Ikọ̀ ọmọ ogun Isreali ṣekúpa olórí Hamas, Abu Karim
Ọjọ Aiku, ọjọ keje oṣu Kẹfa ọdun 2026 ni ikọ ologun Israeli sọ eyi di mimọ loju opo X wọn ti wọn ti kede.
Ẹ lo agbára àwọn alálẹ̀ láti ṣẹ́gun ìgbéṣùmọ̀mí - Ooni
Ninu alaye rẹ, Ooni Ogunwusi sọ pe o di dandan fun awọn ọba alaye kaakiri ilẹ Yoruba lati mu agbara iṣẹdalẹ lo.
Ṣé lóòótọ́ ni pé Sunday Igboho ló ṣe bí wọ́n ṣe gba ìtúsílẹ̀ àbúrò Adelabu àtàwọn ọmọ rẹ̀? Ohun tí a mọ̀ rèé
Alẹ ọjọ Satide, ọjọ kẹfa oṣu Kẹfa ọdun 2026 yii ni ileeṣẹ ọlọpaa Naijiria fidi eyi mulẹ, ninu atẹjade ti Alukoro apapọ; DCP Anthony Okon Placid, fi sita l'Abuja.
Ohun tí a mọ̀ rèé nípa ìdúnkokò àwọn agbébọn láti ṣèkọlú sí ilé ẹ̀kọ́ ní Eko
Lara awọn ibi ti wọn darukọ ninu awọn fidio naa pe awọn agbebọn ti balẹ si ni ipinlẹ Eko ni agbegbe Lekki ati Ikorodu ati pe awọn ọlọpaa ti nawọ gan awọn kan ninu awọn agbebọn naa.
Ìdí tí ilé ẹjọ́ fi ní ₦110bn tílé aṣòfin àpapọ̀ fi ra ọkọ̀ ayọ́kẹ́lẹ́, pín fún àjẹmọ́nú wọn, lòdì sófin
Adajọ Yellim Bogoro lo gbe idajọ kalẹ lori ẹjọ ti ajọ ajafẹtọọmọniyan, SERAP pe ẹjọ lori pe ko ba ofin mu bi awọn aṣofin ṣe na owo naa.
Ṣé Adunni Ade onítíátà bímọ fún ọkọ ọlọ́kọ ni, ló ṣe gbé oyún àtọmọ tó bí lọ́dún méjì sẹ́yìn pamọ́? Áláyé rèé
Adunni Ade ṣalaye pe aijẹ kaye mọ nipa oyun atọmọbinrin toun bi ki i ṣe ti pe wọn ko gbọdọ mọ.
Ìgbákejì alága ìjọba ìbílẹ̀ l'Ekiti tí ọlọ́pàá ló jí ara rẹ̀ gbé dèrò àtìmọ́lé
Ogunjọ osu karun ọdun 2026 niroyin kan jade wi pe wọn ti ji arabinrin Ogunleye, igbakeji alaga ijọba ibilẹ ilejemeje gbe lọ nipinlẹ Ekiti.
Èyí lohun tí òfin sọ nípa àwọn tó bá ń gbé ìròyìn ẹlẹ́jẹ̀ pé jàndùkú wọ ìlú àti ìjìyà tó wà fún un
Awọn ipinlẹ ti awọn eeyan ti gbe iroyin ẹlẹjẹ pe agbesunmọmi wọ ilu ati ohun ti ofin sọ nipa pinpin iroyin ẹlẹjẹ.
Ṣé lóòótọ́ ni ọmọbìnrin akẹ́kọ̀ọ́ kan ti kú sígbèkùn ajínigbé nínú àwọn tí wọ́n jí gbé l'Ogbomoso? Àlàyé rèé
Iroyin naa lo tubọ mu ibanujẹ ati ikayasoke wa, bẹẹ ni o da omi tutu si ọkan ọpọ ọmọ Naijiria.
Àwọn ẹgbẹ́ òṣèlú jànkàn tó lè má kópa nínú ètò ìdìbò ọdún 2027
Eyii ko ṣẹyin awọn oniruru ipẹjọ to n waye lẹyin alakalẹ INEC naa.
Oriyomi Hamzat ṣàlàyé àjọsẹpọ̀ rẹ̀ pẹ̀lú Sheikh Gumi, ìgbésùnmọ̀mí àti akatakítí ẹ̀sìn
Ni itẹsiwaju alaye rẹ, Oriyomi Hamzat sọ pe oun ko ṣalaye ọrọ yii nitori ki araalu le dibo foun rara.













































































