BBC News, Yorùbá - Ìròyìn
Ìròyìn tó ṣe kókó
Àwọn ohun tó yẹ kó o mọ̀ nípa St.Janet, akọrin Jùjú tó jáde láyé
Ọmọ ilu Ile Ife, nipinlẹ Osun ni Oloogbe Iyun Omotoyosi Ajilore tawọn eeyan mọ si St. Janet.
Olorì Oluwatosin bímọ obìnrin fún Ooni Ogunwusi lẹ́yìn oṣú mẹ́ta tí Olorì Maryam bí ìbejì
Alekun oore ọmọ yii lo n waye lẹyin oṣu mẹta ti Yeyeluwa, Olori Maryam Ajibola Anako, bi ibeji ọkunrin fun Ooni si ilẹ alawọ funfun.
Ìdí tí a kò fi sin Olóye Lekan Alabi, Abese Olubadan sílùú Ibadan-Tunji Alabi, ọmọ Olóògbé
Ọpọ eeyan lo n beere pe ki lo le ṣẹlẹ ti agba oye ilẹ Ibadan yoo lọ sun oorun ayeraye rẹ niluu Fiditi, dipo ilẹ Ibadan ti wọn ti bi i.
Lẹ́yìn iná tó ṣẹ́yọ ni pápákọ òfurufú Murtala Muhammed l'Eko, iṣẹ́ bẹ̀rẹ̀ padà
Ṣaaju ni FAAN ti fi atẹjade to kede iṣẹlẹ ina naa lede laaarọ ọjọ Aiku naa ti I ṣe ọjọ keji oṣu Kẹjọ ọdun 2026.
Owó ìrànwọ́ iná mọ̀nàmọ́ná tí ìjọba fẹ́ẹ́ yọ kúró ní 2027, ohun tí a mọ̀ rèé
Minisita to n ri si ọrọ ina mọnamọna ni Naijiria, Joseph Tegbe, ṣalaye pe igbesẹ yii ṣe pataki lati ri i pe ina ọba duro deede fun araalu lati ri lo.
Ìwádìí bẹ̀rẹ̀ lórí fídíò tó ṣàfihàn báwọn ọlọ́pàá kan ti ṣe ìkọlù sí ọ̀dọ́kùnrin tó ń ta góòlù l'Eko
Ọlọpaa sọ pe ẹkun E (Area E) ni awọn ọlọpaa naa ti n ṣiṣẹ, ti a si gbọ pe asiko ti ọkunrin oni goolu naa fẹẹ lọ gbe ọja goolu fun onibara rẹ ni wọn da a duro lati ṣe ikọlu si i.
Ìdí rèé tí ìgbéyàwó méjì tí mó ṣe fi foríṣánpọ́n àti bí mi ò ṣe tí ì fé ìyàwó míì- Mr Steeze
Farooq Oreagba sọ pe ''ẹmeji ni mo ti fẹ iyawo, iyawo ti mo kọkọ fẹ si ni ọrẹ korikosun mi titi di oni.''
Àlàyé lórí bí Tinubu ṣe fi ìwé ẹ̀rí fásítì rẹ̀ nìkan ṣọwọ́ sí INEC tó sì kùnà láti fi ìwé ẹ̀rí alákọ̀ọ́bẹ̀rẹ̀ àti girama ránṣẹ́
Ajọ INEC lo gbe awọn iwe ti Tinubu buwọ lu, to fi mọ awọn iwe ẹri rẹ soju opo wọn lọjọ Abamẹta to kọja yii, fun gbogbo eeyan lati ri.
Mọ̀ nípa ìrẹsì tó léwu fún ìlera rẹ tí àjọ NAFDAC ń kìlọ̀ rẹ̀
Awọn ohun to lewu gidi fun ara (metallic contamination) lo wa ninu irẹsi naa lẹyin tawọn oluwadii ṣiṣẹ lori rẹ bi NAFDAC ṣe sọ.
Okocha fi ẹ̀yìn Portable janlẹ̀ nínú ìjà ẹ̀ẹ̀kejì, Ọmọ Olalomi ṣàlàyé bó ṣe jẹ́
Tẹ o ba gbagbe, eyi ni igba keji ti awọn gbajumọ mejeeji yoo wọya ija ẹṣẹ kikan, wọn ti kọkọ jọ ja ri ni 2023 ti Portable si bori.
Ẹgbẹ̀rún kan lé nígba ni àwọn dókítà tó ṣẹ́kù l'Ógùn – NMA pariwo síta
Ẹgbẹ naa ṣekilọ pe alafo naa ti ko ọpọ iṣẹ sori awọn oṣiṣẹ eleto ilera, to si ni ipinlẹ naa nilo ẹgbẹrun marun-un dokita lati pese eto ilera to pe ye.
Wo bí ìtakùrọ̀sọ BBC Yorùbá ṣe lọ láàárín àwọn olùdíje sípò gómìnà ìpínlẹ̀ Osun
Oludije sipo gomina bii Ademola Adeleke, Accord; Bola Oyebamiji, APC; Najeem Salaam, ADC; Olajide Esan ti AAC; Olufẹmi Adesuyi, ZLP ati awọn miran ni BBC pe.
BBC News Yorùbá ti wà lórí ìkànnì WhatsApp
Má jẹ́ kí etí rẹ ó di sí gbogbo ìròyìn ohun tó ń lọ ní Naijiria àti káàkiri àgbáyé. Mọ̀ nípa wọn lórí ìkànnì Whatsapp rẹ
Ìròyìn Àkàgbádùn
Ilé tí àwọn akẹ́kọ̀ọ́ ń gbé dàwó, èèyàn méjì kú, mẹ́ta dèrò ilé ìwòsàn
Akojọpọ awọn adoola ẹmi lati ajọ Red Cross, NEMA, ileeṣẹ adoola ẹmi ipinlẹ Anambra, SEMA, ileesẹ panapa, ileeṣẹ ọlọpaa atawọn adoola ẹmi miran ni wọn wa nibẹ.
Wo àwọn ibi tí Egúngún Olóòlù yóò lọ nílùú Ibadan, àwọn ọjọ́ tí yóò wà láwọn agbègbè náà àti ohun márùn ún tó yẹ kí o mọ̀ nípa Egúngún olóòlù
Ṣaaju asiko yii ni Kabiesi Olubadan, Ọba Rashidi Adewolu Ladoja ti kọkọ kede ninu atẹjade kan pe ki awọn araalu, paapaa awọn obinrin, ṣora fun Egungun naa.
Mo gbọ́ pé àwọn kan láwọn fẹ́ jíbò l'Osun, eré ọmọdé ni, ìbò Osun ò ṣe é fọwọ́ kàn – Gómìnà Adeleke
Oke Ila ni Gomina Adeleke ti sọrọ naa, nijọba ibilẹ Ifedayo, ipinlẹ Osun, lasiko iwọde ipolongo ibo to ku si dẹdẹ naa.
Àlàyé rèé lórí bọ́wọ́ ṣe tẹ afurasí sọ́jà tó ń ta aṣọ ọmọ ogun Naijiria fún áwọn agbésùnmọ̀mí
Afurasi naa, Mohammed Yusuf pẹlu nọmba 23NA/84/1939 Private to n ṣiṣẹ pẹlu ẹka ileeṣẹ ologun to n ran aṣọ awọn ọmogun niluu Eko ni wọn mu ni nnkan bii ago mẹfa aabọ lopin ọsẹ to kọja lẹyin iṣẹ iwadii kan ti ileeṣẹ ologun ṣe.
Ọmọ Nàìjíríà míràn tún kú sọ́wọ́ ọlọ́pàá ní South Africa; Ìjọba Nàìjíríà fárígá, pè fún ìwádìí kíkún
Tẹ o ba gbagbe, South Africa ti n le awọn ajeji rẹpẹtẹ kuro nilẹ naa o ti pẹ, paapaa awọn alawọ dudu ti wọn jẹ ọmọ Africa bii tiwọn, lori ẹsun pe wọn ko je kawọn riṣẹ ṣe niluu abinibi awọn.
Tinubu àti Atiku tún gbéná wojú ara wọn lórí ìgbẹ́jọ́ Tinubu tí iléeṣẹ́ kan gbé dìde ní Amẹ́ríkà
Awuyewuye to n waye lasiko yii laaarin awọn mejeeji ko ṣẹyin bi ileeṣẹ aarẹ ṣe fẹsun kan Atiku pe o n ṣe agbatẹru ileeṣẹ kan ni Amẹrika lati lọ ṣagbedide iwadii lori igbẹjọ ti Tinubu koju ni Amẹrika lọdun 1993.
A kò tí ì fún PFIPC ní kọ́bọ̀ nínú ₦1.3bn tí wọ́n yà sọ́tọ̀ fún un - Ọ́fíìsì ètò ìṣúná
Ọjọ Ẹti, ọjọ kẹrindinlọgbọn oṣu Keje ọdun 2026 yii ni Adari pata nileeṣẹ ijọba naa, Tanimu Yakubu, yọju si igbimọ to n tọpinpin N1.3 billion to wa ninu iṣuna ọdun 2026 fun ileeṣẹ PFIPC.
Àwọn olùgbé Akure pariwo lórí òórùn tó gbalẹ̀ kan, ìjọba bẹ̀rẹ̀ ìwádìí
Ileeṣẹ ijọba ipinlẹ Ondo to n ri ọrọ ayika ti fidi rẹ mulẹ pe iwadii ti fi han pe oorun yii ko ṣẹyin awọn eeyan kan ti wọn n da idọti lọna aitọ sina odo to n ṣan.
Olórí àwọn tó ń pèsè owó fún ẹgbẹ agbésùnmọ̀mí ISWAP ní Naijiria jọ̀wọ́ ara rẹ̀ fún ọmọ ogun
Ninu atẹjade kan, ileeṣẹ ọmọ ogun sọ pe igbesẹ afurasi naa lo n waye lasiko ti pupọ awọn agbesunmọmi bi tirẹ bẹrẹ si n jọwọ ara wọn fun ileeṣẹ ọmọ ogun.
Ẹ wo ilé ìwòsàn táwọn aláboyún ti ń bímọ sórí ẹní
Ile iwosan alabọde Badawa ti dẹnu kọlẹ lati bi ọdun mẹwaa ti atẹgun ojo ti ba apa kan ile iwosan naa jẹ.
America kìlọ̀ fáwọn ọmọ Nàìjíríà tó tún jẹ́ ọmọ America láti má ṣe lo ìwé ìrìnná míràn yàtọ̀ sí ti orílẹ̀èdè náà láti wọlé tábì jáde l'America
Ninu atẹjade kan ti ajọ naa fi lede loju opo X rẹ lọjọ Aiku, ni wọn ti kede pe eyi kan gbogbo ọmọ oniluu l'America pẹlu, titi kan awọn ọmọde to ba ti jẹ ọmọ oniluu meji.
Àfiwé owó oṣù àwọn ṣọ́jà Nàìjíríà pẹ̀lú àwọn akẹgbẹ́ wọn lórílẹ̀èdè míràn ní Áfíríkà
Ilọpo mẹjọ ni owo oṣu awọn ọgagun lorilẹede Naijiria fi kere si ti awọn akẹgbẹ wọn lorilẹede South Africa.
Ìròyìn Pàtàkì
Kọ́milẹ́kọ̀ọ́
Ẹ tẹ̀lé wa lórí ìkànnì ayélujára
Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn
Adeleke pàṣẹ kí àtúnṣe bẹ̀rẹ̀ lórí afárá tó bẹ̀rẹ̀ sí ń yẹ̀ lẹ́yìn ọ̀sẹ̀ mẹ́ta tí wọ́n ṣi nílùú Osogbo
Ọjọ kinni, oṣu Keje, ọdun 2026 yii ni wọn ṣi afara naa amọ o ṣeni laanu pe ko tii to ọsẹ mẹta pere ti wọn ṣi ti apakan rẹ bẹrẹ si n jin wọnu lẹyin ojo arọrọda kan.
Wo àwọn adarí ẹgbẹ́ NURTW tí wọ́n ti gbẹ̀mí wọn nílùú Eko
Eyii ni akojọpọ awọn kan lara awọn adari NURTW ti wọn ti ṣekua niluu Eko.
Àlàyé rèé lórí bí eégún Olóòlù ṣe dé Ibadan, ìdí tí kìí fi wọ bàtà tàbí fojú kan obìnrin
Ní kété tí ènìyàn bá ti dárúkọ eégún Oloolu ní Ibadan, kálukú yoo máa forí gbárí, torí ẹ̀rù àti agbára tó wà lára rẹ̀
Kí ló dé tí orin K1 "Tó bá lóyún kóyún, sàárà ni" fi ń mi orí ayélujára tìtì? Àlàyé rèé
Arabinrin toun ni oun bimọ fun K1 sọ pe oun lọ ba mama K1 lori ọrọ ọmọ oun Azizat, mama si ṣe bi abiamọ nigba ti wọn ri ọmọ naa.
Ẹkún sọ níbí ìsìn ìrántí fún olóògbé John Olaleye olùkọ́ Oriire táwọn jàndùkú ajínigbé ṣekúpa
Ti ẹ o ba gbagbe, ọjọ Aiku akọkọ oṣu kẹfa ọdun yii ni awọn agbebon ọhun sẹkupa Ọgbẹni Olaleye, gẹgẹ bi giwa ile ẹkọ girama, Ahoro Esinele, iyẹn, Arabinrin Rachael Alamu ṣe fi idi rẹ mulẹ.
Ìbanilórúkọjẹ́ lẹ̀sùn ìkówójẹ tí wọ́n fi kàn mí, Oluomo sọ̀rọ̀ lẹ́yìn tílé aṣòfin Ogun fagilé ẹ̀sùn tí wọ́n fi kan adarí ilé tẹ́lẹ̀
Ile tun fẹnuko nibi ijokoo wọn lonii Ọjọru niluu Abeokuta wi pe iyọnipo rẹ ti di ikọwefiposilẹ bayii.
Mi ò lérò pé mo lè dé ipò Ìmáàmù ìlú Ilorin, àmọ́, mo ti máa ń rí àwọn àpẹẹrẹ kan tipẹ́ - Ìmáàmù Ilorin tuntun
Imaamu Ilorin tuntun fikun ọrọ rẹ pe awọn musulumi ko gbọdọ jẹ ki ero awọn ọta Islam to maa n sọ pe ẹsin jagidijagan ni ẹsin Islam ṣẹ mọ wọn wa lara.
Ọlọ́pàá mẹ́rin tó bèèrè owó ẹ̀yìn lọ́wọ́ awakọ̀ lọ́nà márosẹ̀ Ọrẹ si Benin wọ gàù, ilé-iṣẹ́ ọlọ́pàá bẹ̀rẹ̀ ìwádìí lórí wọn
Gẹgẹ bi kọmandi ọlọpaa Ondo ṣe wi loju opo X, wọn ti mọ awọn ọlọpaa to wa ninu fidio yii, iwadii ati igbesẹ to yẹ si ti bẹrẹ lorii wọn.
Kókó ìpàdé Sẹ́nẹ́tọ̀ Folarin pẹ̀lú Ààrẹ Tinubu lórí awuyewuye nípa olùdíje sípò gómìnà fẹ́gbẹ́ APC ní ìpínlẹ̀ Oyo
Ipade naa ni wọn lo da lori erongba lati fi opin si gbogbo aawọ, wahala ati ikunsinu to wa laaarin awọn agbaagba ati alẹnulọrọ ẹgbẹ APC nipinlẹ Oyo, ṣaaju eto idibo gomina to fẹẹ waye ninu oṣu Keji, ọdun 2027.
Mo Bimpe lérí láti gbé àwọn tó ní Lateef Adedimeji kọ́ ni bàbá àwọn ọmọ rẹ̀ lọ sílé ẹjọ́
Lori ayelujara ni iroyin to ni Lateef Adedimeji kọ ni baba awọn Ibẹta ti n tan kalẹ
Fọ́nrán bí Abacha ṣe kú wà lọ́wọ́ mi, arúmọjẹ lásán ni ìtàn táwọn kan ń kọ sínú ìwé kiri - Al-Mustapha, olórí ẹ̀ṣọ́ aláàbò fún Abacha
Latigba ti iku Ọgagun Abacha ti jade sita, ni ariyanjiyan ti wa kaakiri agbaye, paapaa nilẹ Naijiria to ti jẹ adari, ti awọn eeyan ko si gbagbe titi di asiko yii.
Kílódé tí àwọn èèyàn ń fi ohùn ránṣẹ́ sí Gheghe lórí ayélujára?
Gheghe gbajumọ fun awọn ọrọ to maa n sọ lori ayelujra fun awọn ọkunrin lori bi wọn ko sẹ gbọdọ maa na owo wọn fun obinrin.















































































