Kò ṣe é má gbọ̀ ọ́

Àkọlé fọ́nrán ohùn, Ko see ma gboo
Kò ṣe é má gbọ̀ ọ́
Published

Níṣe lọrọ di ẹni ori yọ o dile

Bawọn ọmọ ẹgbẹ oṣelu All Progressives Congress, APC nipinlẹ Oyo ṣe yawọ ile ẹgbẹ naa to wa ni Oke Ado ni ilu Ibadan

Ti wọn si bẹrẹ si ni ṣekọlu sawọn oludije atawọn alaṣẹ

Bi wọn ṣe ni awọn igbesẹ kan ti wọn n gbe ko tẹ awọn lọrun

Ẹkunrẹrẹ wa loju opo wa

xxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxx

Ajọ to n ri si iwa ajẹbanu ni Naijiria, EFCC

Ti wọn gbajumọ ori ayelujara, Blessing CEO lọ sile ẹjọ

fẹsun pe o parọ gbowo milọnu mẹrindinlogoji naira lọwọ obinrin kan pe oun fẹ gbe ile fun ni Lekki

Amọ to da owo naa sapo ti ko si gbele kankan fun ẹni naa

Ka a loju opo bbc.com/Yoruba

xxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxx

Eeyan marundinlaadọrin jade laye

Bi aarun ebola ṣe tun ṣuyọ ni DR Congo

Ajọ to n ri si ajakalẹ aarun ilẹ Africa Centres for Diseases Control and Prevention, CDC

Ni eeyan to le nigba lo ti lugbadi aarun naa bayii

To o ba fẹ mọ bo o ṣe le da aabo bo ara rẹ lọwọ ebola