Kò ṣe é má gbọ̀ ọ́
Níṣe lọrọ di ẹni ori yọ o dile
Bawọn ọmọ ẹgbẹ oṣelu All Progressives Congress, APC nipinlẹ Oyo ṣe yawọ ile ẹgbẹ naa to wa ni Oke Ado ni ilu Ibadan
Ti wọn si bẹrẹ si ni ṣekọlu sawọn oludije atawọn alaṣẹ
Bi wọn ṣe ni awọn igbesẹ kan ti wọn n gbe ko tẹ awọn lọrun
Ẹkunrẹrẹ wa loju opo wa
xxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxx
Ajọ to n ri si iwa ajẹbanu ni Naijiria, EFCC
Ti wọn gbajumọ ori ayelujara, Blessing CEO lọ sile ẹjọ
fẹsun pe o parọ gbowo milọnu mẹrindinlogoji naira lọwọ obinrin kan pe oun fẹ gbe ile fun ni Lekki
Amọ to da owo naa sapo ti ko si gbele kankan fun ẹni naa
Ka a loju opo bbc.com/Yoruba
xxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxxx
Eeyan marundinlaadọrin jade laye
Bi aarun ebola ṣe tun ṣuyọ ni DR Congo
Ajọ to n ri si ajakalẹ aarun ilẹ Africa Centres for Diseases Control and Prevention, CDC
Ni eeyan to le nigba lo ti lugbadi aarun naa bayii
To o ba fẹ mọ bo o ṣe le da aabo bo ara rẹ lọwọ ebola