BBC News,
Yorùbá
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀
Ìròyìn
Wò
Gbọ́
Àwọn abala
Ìròyìn
Idibo Naijiria 2027
Eré ìdárayá
Èyí to gbajúmọ̀ jù
Idibo Naijiria 2027
Eré ìdárayá
Èyí to gbajúmọ̀ jù
Orilẹede Naijiria
Orí mi ni Garuba fẹ́ gé féú, ọwọ́ tí mo fi dáàbòbo ara mi, ló padà fi àdá ọwọ́ rẹ̀ gé – Adájọ́ tí olújẹ́jọ́ fi àdá gé lọ́wọ́ lásìkò ìgbẹ́jọ́ sọ̀rọ̀ síta
10 Owewe 2026
1:00
Orin,
Kò ṣe é má gbọ̀ ọ́
, Duration 1,00
10 Owewe 2026
2:56
Fídíò,
'Ọ̀nà wà láti ìlú wa lọ sí ọ̀run, egúngún kò sì gbọdọ̀ wọ ìnú ìlú wa'- Èyí ni ìlú tí a kò tí gbọ́dọ̀ ṣe ògùn owó tàbí sun àgbàdo tà
, Duration 2,56
10 Owewe 2026
Kí ló dé tí iléeṣẹ́ ọmọogun fi gbé adarí ikọ̀ tó ń gbógun ti Boko Haram àtàwọn agbébọn kúrò pẹ̀lú àwọn ọ̀gágun 15 míràn? Ohun tí a mọ̀ rèé
10 Owewe 2026
Mo pinnu láti fi Ogogo ṣe olùbádámọ̀ràn pàtàkì nínú ìjọba mi tí mo bá di gómìnà – Yayi
9 Owewe 2026
Kò sí ẹni tó gbà mí gbọ́ pé mi ò kì ń mu sìgá tàbí fa igbó gẹ́gẹ́bí akọrin Fuji - Yeye Qibla onimama
9 Owewe 2026
'Aago meji oru ni mo dele; ọ́fíìsì ni màá sùn lọjọru' - aráàlú kojú ìnira, ìdádúró ọ̀pọ̀ wákàtí lópópónà Eko sí Ibadan nítorí àtúnṣe afárá Kara, ìgbà tí yóò parí
9 Owewe 2026
Wo bí ètò ìsínkú gbajúmọ̀ òṣèré tíátà, Temitope Osoba tó jáde láyé láìpẹ́ yìí yóò ṣe lọ
9 Owewe 2026
Ṣé lóòótọ́ ni wọ́n lẹ òkò mọ́ Peter Obi ní Benue? Ohun tí a mọ̀ rèé
8 Owewe 2026
4:32
Fídíò,
'Ibi alálàájì tó gẹṣin lọ Jumat lọmọ mi lọ tí wọ́n fi jíi gbé, bí mo ṣe ríi lẹ́yìn ọdún kan àti oṣù méjì rèé'
, Duration 4,32
8 Owewe 2026
Kí ló dé tí àwọn ẹ̀yà Tigray ní Ethiopia ṣe ń sọ pé àgbà Olóyè Obasanjo kò tolé?
8 Owewe 2026
Kí ló ṣokùnfà ikú gbajúmọ̀ òṣèrèbìnrin, Nimmy Ferrari tó jáde láyé lásìkò tó ń palẹ̀mọ́ láti ṣí ilé tuntun tó kọ́?
8 Owewe 2026
Ṣé lóòótọ́ ni Tinubu buwọ́lù ẹ̀wọ̀n gbére fáwọn akẹ́kọ̀ọ́ tó bá kùnà láti dá owóòyá NELFUND padà fún ìjọba? Àlàyé rèé
7 Owewe 2026
Mo fẹ lọ fún ìsinmi díẹ̀ kí ara lè tù mí láti lé sin àwọn èèyàn Osun dáadáa - Gómìnà Adeleke
7 Owewe 2026
5:02
Fídíò,
Àwọn kan fẹ́ kí n sọ ₦25 milíọ̀nù tí Ogogo tọ́jú sọ́wọ́ mi di owó Mọ́ṣáláṣí ṣùgbọ́n mo ní rárá – Ìmáàmù ìlú Ilaro
, Duration 5,02
7 Owewe 2026
Wo àwọn alága EFCC tẹ́lẹ̀rí tí wọ́n ti fẹ̀sùn ìwà ìbàjẹ́ kàn
6 Owewe 2026
'Mo wá sí Naijiria láti kojú ọmọ Yahoo tó fẹ́ lu ìyá mi ni jìbìtì àmọ́ ohun tí mo bábọ̀ rèé'
6 Owewe 2026
NRC àti NSCDC dá ìgbìyànjú fífọ́ àti jíjí ohun èlò ojú irin dúró l'Osun
5 Owewe 2026
Àlàyé rèé lórí bí a ṣe ṣàwárí, dóòlà àwọn tí ajínigbé gbé ní Oriire, ọ̀nà táwọn èèyàn mẹ́sàn-án gbà kú àti ọ̀pọ̀ òfegè ìròyìn nípa ìṣẹ̀lẹ̀ náà - Ọ̀gá DSS
4 Owewe 2026
Ilé aṣojú-ṣòfin rí àpò àṣùwọ̀n owó 58 tó so mọ́ Adeniyi Adeyemi, bó ṣe wẹ Gbajabiamila mọ́ pé kò mọwọ́-mẹsẹ̀ nípa ayédèru iléeṣẹ́ PFIPC
3 Owewe 2026
Kí ló fa ikú pásítọ̀ ìjọ Celestial kan àti ìyàwó rẹ̀ lẹ́yìn tí wọ́n jà tán? Àlàyé rèé
3 Owewe 2026
2:00
Fídíò,
Ṣé òótọ́ ni pé àwọn Kristẹni nìkan làwọn jàndùkú agbébọn ń kọlù ní Naijiria?
, Duration 2,00
3 Owewe 2026
Ìdí rèé tí Uber fi kógbá wọlé ní Naijiria lẹ́yìn ọdún méjìlá tó fi ṣe okòwò ọkọ̀ èrò
3 Owewe 2026
Àlàyé rèé lórí bí ògbóǹtarìgì agbésùnmọ̀mí, Muhammadu-Filani, ṣe rí ikú hé lọ́dọ̀ ológun tó gba onírúurú ìbọn lọ́wọ́ rẹ̀
2 Owewe 2026
Page
1
nínú
40
1
2
3
4
5
6
7
40
Tókàn
You might also like:
news
|
sport
|
weather
|
worklife
|
travel
|
future
|
culture
|
world
|
business
|
technology