BBC News,
Yorùbá
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀
Ìròyìn
Wò
Gbọ́
Àwọn abala
Ìròyìn
Eré ìdárayá
Èyí to gbajúmọ̀ jù
Eré ìdárayá
Èyí to gbajúmọ̀ jù
Ofin
Fídíò tó ṣàfihàn ibùba ajínigbé ní ìpínlẹ̀ Ogun - Ohun tí a mọ̀ rèé
26 Ìgbé 2026
Ọwọ́ tẹ afurasí tó yìnbọn níbi àpèjẹ akọ̀ròyìn tí Trump wá nílùú Washington
26 Ìgbé 2026
Ìgbẹ́jọ́ ọmogun 36 tí wọ́n fẹ̀sùn kàn pé wọ́n fẹ́ dìtẹ̀ gbàjọba Tinubu bẹ̀rẹ̀ nílé ẹjọ́ iléeṣẹ́ ológun Naijiria
24 Ìgbé 2026
Gbọin-gbọin ni a wà lẹ́yìn Makinde bí òkè, àhesọ ọ̀rọ̀ lásán n'ìròyìn tó ní a fẹ́ yọ ọ́ nípò – Ilé Aṣòfin Oyo
23 Ìgbé 2026
Ẹ foríjìn mí, mo ṣetán láti d'ówó padà f'áwọn tó bá fẹ́ gbowó tí wọ́n dá fún mi - Blessing CEO
22 Ìgbé 2026
Kí ló ṣẹlẹ̀ tí ọ̀gá ọlọ́pàá 167 fi ń sọ tẹnu wọn níwájú ìgbìmọ̀ tó ń ṣèbáwí ọlọ́pàá? Àlàyé rèé
22 Ìgbé 2026
Bàbá kan yìnbọn pa ọmọ rẹ̀ méje àti ọmọ ọlọ́mọ kan
21 Ìgbé 2026
3:51
Fídíò,
Wọ́n kó Rasheed mérò níbi ìwọ́de EndSARS lọ́dún 2020, ọdún mẹ́fà ló lò lẹ́wọ̀n
, Duration 3,51
20 Ìgbé 2026
Ademola Adeleke pe ilé ìfowópamọ́ UBA àtàwọn alága kánsù APC lẹ́jọ́
18 Ìgbé 2026
Ìjọba Kwara pe Bukola Saraki, Abdulfatah Ahmed àtàwọn mìí lẹ́jọ́ ẹ̀sùn ìpànìyàn
18 Ìgbé 2026
Ipa wo ni àìsí aṣojú INEC níbi ìpàdé àpérò ADC yóò ní lórí ẹgbẹ́ òṣèlú náà?
16 Ìgbé 2026
Àlàyé rèé lórí ìdí tí ìjọba ṣe yọ ẹ̀sùn fifi owó ṣèrànwọ́ fún ìgbẹ́sùnmọ̀mí kúrò nínú ẹjọ́ ti Malami ń jẹ́
16 Ìgbé 2026
Kí ni alága àjọ INEC ṣe tí MURIC ṣe yarí pé lílọ ni yóò lọ àmọ́ táwọn ọ̀dọ́ ìlú rẹ̀ ṣèwọ́de àtìlẹ́yìn fún un?
15 Ìgbé 2026
"Bí Ishmail tí iná gbé ní Ilorin ṣe ń kàwé, ló ń ṣiṣẹ́ láti jẹ́ èèyàn láyé, owó díẹ̀ tó rí ló fi ra Kọ̀ǹpútà tó gbiná"
15 Ìgbé 2026
Èèyàn bíi 400 rí ẹ̀wọ̀n he lórí ìbáṣepọ̀ wọn pẹ̀lú agbésùnmọ̀mí ní Naijiria
12 Ìgbé 2026
''Mi ò sọ pé àṣìṣe wà nínú òfin owó orí tuntun ilẹ̀ Nàìjíríà, wọ́n ṣì mí gbọ́ ni'' -Mínísítà ìpínlẹ̀ fún ètò ìṣúná
12 Ìgbé 2026
Ìdílé oyè fún Gómìnà Adeleke ní gbèdéke ọjọ́ méje láti rọ Apetumodu tó ń ṣẹ̀wọ̀n l'Ámẹ́ríkà lóyè
10 Ìgbé 2026
4:00
Fídíò,
Soun Ogbomoso ti pín ìlú yẹ́lẹyẹ̀lẹ pẹ̀lú ìwà kíìgbọ́-kìígbà rẹ̀, èmi ò sì lè báa ṣiṣẹ́ mọ́ ni mo ṣe kọ̀wé fipò Máyégún sílẹ̀ -Sẹ́nétọ̀ Adeseun
, Duration 4,00
10 Ìgbé 2026
Ọkùnrin kan ṣekúpa èèyàn mẹ́ta nínú ìdílé kan náà, ariwo sọ
10 Ìgbé 2026
Ilé ẹjọ́ gbẹ́sẹ̀ lé ilẹ̀, ilé ìtura, àtàwọn dúkìá míì tí wọ́n ní pásítọ̀ fi ọ̀nà èrú kó jọ
4 Ìgbé 2026
Kí ló dé tí ìjọba àpapọ̀ fi ₦9trn kún owó ìṣúná ọdún 2026?
3 Ìgbé 2026
ADC ní alága INEC ti gbàbọ̀dè, awọn fẹ́ kó kọ̀wé fipò sílẹ̀, APC fèsì pé kò sẹ́ni tó kó ba wọn, fúnra ara wọn, ni wọ́n ń ṣera wọn
3 Ìgbé 2026
Àwọn ìgbésẹ̀ wo ló yẹ fún iléeṣẹ́ ìbánisọ̀rọ̀ láti gbé kí wọ́n tó ta síìmù ìpè ti ẹnìkan ti lò rí fún ẹlòmíì?
1 Ìgbé 2026
ICPC tú El-Rufai sílẹ̀ lẹ́yìn tó pàdánù ìyá rẹ̀
28 Ẹrẹ̀nà 2026
Page
1
nínú
40
1
2
3
4
5
6
7
40
Tókàn
You might also like:
news
|
sport
|
weather
|
worklife
|
travel
|
future
|
culture
|
world
|
business
|
technology