BBC News,
Yorùbá
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀
Ìròyìn
Wò
Gbọ́
Àwọn abala
Ìròyìn
Eré ìdárayá
Èyí to gbajúmọ̀ jù
Eré ìdárayá
Èyí to gbajúmọ̀ jù
Ojude Ọba 2019: Àwọn èèkàn lórílẹ̀-èdè Nàìjíríà ti péjú fún ayẹyẹ ojúde Ọba
Àkọlé àwòrán,
Ojude Oba tí ọdún yìí ti gbéra sọ pẹ̀lú oníruuru àwọn aṣọ alárànbara yorùba to ń wúni lóri, Awọn ẹgbẹ́ Tobalàṣẹ obinrin rèé nínú àṣọ okè aláwọ̀ ewé
Published
13 Ògún 2019
'Kò sí ohun tó burú nínú bí Ajimobi ṣe dá Yewande tó pa ọkọ rẹ̀ sílẹ̀'
Àwọn Fadá mẹ́rin gbà itusílẹ̀ lọwọ àwọn ajínigbé
Samuel Okwaraji: Ó pé ọgbọ̀n ọdún tí lónìí ti akọni àgbábọ̀ọ̀lù papo dà
Ẹ ṣe àwárí ọdànran tó bọ mọ́ọ yín lọ́wọ́ - Turkur Buratai
Àkọlé àwòrán,
Gbogbo àwọn ọmọ ẹgbẹ́ Gbobaniyi lókùnrin àti lóbìrin ló ti lọ ki ọba aláde lóri ìjòkò
Àkọlé àwòrán,
Lẹ́gbẹ́ lẹ́gbẹ́ ni gbogbo àwọn ti wọ́n péju síbi ayéyé Ojude Oba tí ọdún 2019
Àkọlé àwòrán,
Tokùnrin tobinrin ló wọsọ ìgbà níbi àyẹyẹ ojude oba tọdún yìí, Ẹgbẹ́ Bọbakẹ́yẹ Ọkunrin ni àwọn yìí
Àkọlé àwòrán,
Tarúgbó tomidàn ló wà nibi àyẹyẹ yìí, gbogbo oju wọ́n lo gúrégé pèlú, àwọn ẹgbẹ́ bọ́bakẹ́yẹ obinrin rèé
Àkọlé àwòrán,
Gbogbo àwọn olóyè àti èèkàn ìlú ló péjú
Àkọlé àwòrán,
Kìí ṣe àwọn ẹgbẹ́ gbẹ́ jọdá nìkàn ló péju, àwọn ọdọ náà jáde wá láti yẹ́ àṣ]a ìbílẹ̀ sí
Àkọlé àwòrán,
Aláàfin Ọyọ, ikú bábá yèyé, Ọba Lamidi Adeyemi náà péjú síbi ayẹyẹ ojúde Oba ní'lú Ijebu
Àkọlé àwòrán,
Gómínà ìpínlẹ̀ Ogun, Dapo Abiodun àti Awùjalẹ̀ Ijẹ̀bú Ọba Sikiru Adetona
Àkọlé àwòrán,
Gómìnà tẹ́lẹ̀rí ní ìpínlẹ̀ Ogun, Ọtunba Gbẹnga Daniels
Àkọlé àwòrán,
Ẹgbẹ́ Bọ́baguntẹ ilẹ̀ Ijẹbu
Àkọlé àwòrán,
Gbogbo ojú tó ti ríra típẹ tún ni àànfàni láti ṣe "Ẹ k;u àti"
Àkọlé àwòrán,
Ẹgbẹ́ Obafunwaji Obinrin Adedoyin rèé nínú aṣọ ofi aláwọ̀ búlù
Àkọlé àwòrán,
Ẹgbẹ́ Tobalaṣẹ Ọkunrin náà ko gbẹ́yìn
Àkọlé àwòrán,
Gbogbo àwọn ọmọ ẹgbẹ́ Gbobaniyi lókùnrin àti lóbìrin ló ti lọ ki ọba aláde lóri ìjòkò
Skip Móríwú and continue reading
Móríwú
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ
03:05
Fídíò,
"Ìdájọ́ ikú tí wọ́n dá fún àwọn tó kọlu ṣọ́ọ̀ṣì Owo kò dá ọmọ mi àti àbúrò mi méjì tí wọ́n pa padà"
, Duration3,05
01:27
Fídíò,
Bí o bá ń pẹ́ kí o tó sùn lálẹ́, ewu ń bẹ fún ìlera ọpọlọ rẹ
, Duration1,27
04:11
Fídíò,
Bàbá mi ló pàṣẹ fún mi lójú àlá pé kí n máa múra bí ọkùnrin – Funmilayo Elemure Ogunyemi
, Duration4,11
00:37
Fídíò,
Aráàlú fárígá, ṣèwọ́de ní Ibadan tako ìjọba lórí bí àwọn akẹ́kọ̀ọ́ àti olùkọ́ tí wọ́n jí gbé ṣì ṣe wà ní àhámọ́
, Duration0,37
02:45
Fídíò,
Ìfúpá àwọn èèyàn Ayetoro l‘Ondo ń ga sí, torí bí òkun ṣe ń ya wọ ìlú, gbé iléẹ̀kọ́, ilégbèé, iléeṣẹ́, ilẹ̀ àti ibojì òkù lọ
, Duration2,45
01:26
Fídíò,
Wo àkóbá mọ́kànlá tí ohun mímu ‘Energy Drinks’ le ṣe fún àgọ́ ara rẹ
, Duration1,26
04:32
Fídíò,
Ìjì òjò líle sí òrúlé, da ògiri wó nílé ẹ̀kọ́ girama ọgbọ̀n l‘Ogbomoso, àwọn akẹ́kọ̀ọ́ n kẹ́kọ̀ọ́ lábẹ́ ilé àlàpa
, Duration4,32
02:16
Fídíò,
"Ìjọba rí epo rọ̀bì ní ìlú wa àmọ́ a kò jàǹfààní kankan, kò sí omi, iná, ojú ọ̀nà, ààbò, iléẹ̀kọ́ àti ilé ìwòsàn"
, Duration2,16
03:22
Fídíò,
Àwọn ajínigbé tó kó àwọn akẹ́kọ̀ọ́ yìnbọn sí wa nígbà tí a ń lé wọn wọgbó ìbọn wà kò ràn wọ́n ni – Àwọn ọlọ́dẹ ìlú Esinele
, Duration3,22
02:31
Fídíò,
Wo ohun tó yẹ kí o mọ̀ nípa àrùn Ebola tuntun
, Duration2,31
02:34
Fídíò,
Oronna, jagunjagun tó gbéra láti Oyo lọ tẹ ìlú Ilaro dó
, Duration2,34
End of Móríwú
Ìròyìn tó ṣe kókó
Ohun tí a mọ̀ rèé lórí àwọn agbébọn tí wọ́n ní wọ́n ti wọ ìpínlẹ̀ Eko
6 Òkùdu 2026
Oriyomi Hamzat ṣàlàyé àjọsẹpọ̀ rẹ̀ pẹ̀lú Sheikh Gumi, ìgbésùnmọ̀mí àti akatakítí ẹ̀sìn
6 Òkùdu 2026
Àwọn ẹgbẹ́ òṣèlú jànkàn tó lè má kópa nínú ètò ìdìbò ọdún 2027
6 Òkùdu 2026
Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn
''Tí ìjọba bá lè gba ọmọ Yoruba láyè láti lo ìlànà ti ìbílẹ̀, ilẹ̀ wa yóò bọ́ lọ́wọ́ agbéṣùnmọ̀mí''
31 Èbibi 2026
'A ò lè lọ síbi iṣẹ́ mọ́ torí àwọn olùkọ́ àtàwọn akẹ́kọ̀ọ́ tí wọ́n jí gbé l'Ogbomoso,' àwọn olùkọ́ ṣèfẹ̀hónúhàn l'Oyo
30 Èbibi 2026
Agbébọn jí ajagunfẹ̀yìntì àti ìyàwọ rẹ̀ gbé ní Katsina
31 Èbibi 2026
Báwo ni ayẹyẹ Ojude Oba 2026 ṣe rí láì sí Awujale Ijebu lórí oyè? Ohun tó ṣẹlẹ̀ níbẹ̀ rèé
30 Èbibi 2026
"Ẹ jọ̀ọ́ ẹ má jẹ́ kí wọ́n fi ẹ̀mí wa ṣòfò," àwọn olùkọ́ tí agbésùnmọ̀mí jígbé l'Ogbomoso rawọ́ ẹ̀bẹ̀ sí ìjọba
30 Èbibi 2026
Ilé ìgbìmọ̀ àṣofin Ghana buwọ́lu òfin tó kéde ẹ̀wọ̀n ọdún mẹ́ta fún ìbálòpọ̀ akọsákọ àti abosábo
30 Èbibi 2026
Àgbà òṣèré tíátà, Feso Oyewole jáde láyé
30 Èbibi 2026
Taa ni Balogun Kuku, bàbá olówó tó mú ẹ̀sìn Islam wọ ilẹ̀ Ijebu, tó tún bẹ̀rẹ̀ ọdún Ojude Ọba?
28 Èbibi 2026
Àlàyé rèé lórí bí fọ́nrán ohùn Tinubu tí wọ́n fi AI ṣe, ṣe dá wàhálà sí VDM lọ́rùn, tí wọn ṣí ló gbọdọ̀ fojú winá òfin
28 Èbibi 2026
Ìròyìn tí àwọn ènìyàn fẹ́ràn jùlọ
1
Ṣé lóòótọ́ ni ọmọbìnrin akẹ́kọ̀ọ́ kan ti kú sígbèkùn ajínigbé nínú àwọn tí wọ́n jí gbé l'Ogbomoso? Àlàyé rèé
2
Ohun tí a mọ̀ rèé lórí àwọn agbébọn tí wọ́n ní wọ́n ti wọ ìpínlẹ̀ Eko
3
Oriyomi Hamzat ṣàlàyé àjọsẹpọ̀ rẹ̀ pẹ̀lú Sheikh Gumi, ìgbésùnmọ̀mí àti akatakítí ẹ̀sìn
4
Àwọn ẹgbẹ́ òṣèlú jànkàn tó lè má kópa nínú ètò ìdìbò ọdún 2027
5
Èyí lohun tí òfin sọ nípa àwọn tó bá ń gbé ìròyìn ẹlẹ́jẹ̀ pé jàndùkú wọ ìlú àti ìjìyà tó wà fún un
6
Adájọ́ kú sórí òrùlé Ṣọ́ọ̀ṣì lẹ́yìn tí wọ́n ní ó pa ìyàwó rẹ̀, tún bá òkú rẹ̀ sún lójú àwọn ọmọ wọn
Tí a mú dójú ìwọ̀n gbẹ̀yìn ní: 11 Ọ̀pẹ̀̀ 2022
7
Mo máa dárúkọ àwọn olóṣèlú tó ṣagbátẹrù ìjinigbé àwọn akẹ́kọ̀ọ́ l'Ogbomoso tí wọn kò bá jáwọ́ - Igboho
8
Irọ́ ńlá! kò sí "Hacker" kankan ò kọlu ẹ̀rọ ayélujára wa o, nọ́mbà yín wà ní ṣẹpẹ́ - Àjọ NIMC
Tí a mú dójú ìwọ̀n gbẹ̀yìn ní: 11 Sẹ́rẹ́ 2022
9
Seyi Makinde ni yóò ṣojú wa nínú ètò ìdìbò Ààrẹ ọdún 2027 – Ẹgbẹ́ òṣèlú APM
10
Ọkọ̀ dáńfó tí mò ń wà ní mo fi kọ́lé, rán ọmọ mẹ́ta ní fásitì - Obìnrin àkọ́kọ́ tó ń wa dáńfó l‘Eko
Tí a mú dójú ìwọ̀n gbẹ̀yìn ní: 20 Èrèlè 2020
You might also like:
news
|
sport
|
weather
|
worklife
|
travel
|
future
|
culture
|
world
|
business
|
technology