BBC News,
Yorùbá
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀
Ìròyìn
Wò
Gbọ́
Àwọn abala
Ìròyìn
Idibo Naijiria 2027
Eré ìdárayá
Èyí to gbajúmọ̀ jù
Idibo Naijiria 2027
Eré ìdárayá
Èyí to gbajúmọ̀ jù
Ojude Ọba 2019: Àwọn èèkàn lórílẹ̀-èdè Nàìjíríà ti péjú fún ayẹyẹ ojúde Ọba
Àkọlé àwòrán,
Ojude Oba tí ọdún yìí ti gbéra sọ pẹ̀lú oníruuru àwọn aṣọ alárànbara yorùba to ń wúni lóri, Awọn ẹgbẹ́ Tobalàṣẹ obinrin rèé nínú àṣọ okè aláwọ̀ ewé
Published
13 Ògún 2019
'Kò sí ohun tó burú nínú bí Ajimobi ṣe dá Yewande tó pa ọkọ rẹ̀ sílẹ̀'
Àwọn Fadá mẹ́rin gbà itusílẹ̀ lọwọ àwọn ajínigbé
Samuel Okwaraji: Ó pé ọgbọ̀n ọdún tí lónìí ti akọni àgbábọ̀ọ̀lù papo dà
Ẹ ṣe àwárí ọdànran tó bọ mọ́ọ yín lọ́wọ́ - Turkur Buratai
Àkọlé àwòrán,
Gbogbo àwọn ọmọ ẹgbẹ́ Gbobaniyi lókùnrin àti lóbìrin ló ti lọ ki ọba aláde lóri ìjòkò
Àkọlé àwòrán,
Lẹ́gbẹ́ lẹ́gbẹ́ ni gbogbo àwọn ti wọ́n péju síbi ayéyé Ojude Oba tí ọdún 2019
Àkọlé àwòrán,
Tokùnrin tobinrin ló wọsọ ìgbà níbi àyẹyẹ ojude oba tọdún yìí, Ẹgbẹ́ Bọbakẹ́yẹ Ọkunrin ni àwọn yìí
Àkọlé àwòrán,
Tarúgbó tomidàn ló wà nibi àyẹyẹ yìí, gbogbo oju wọ́n lo gúrégé pèlú, àwọn ẹgbẹ́ bọ́bakẹ́yẹ obinrin rèé
Àkọlé àwòrán,
Gbogbo àwọn olóyè àti èèkàn ìlú ló péjú
Àkọlé àwòrán,
Kìí ṣe àwọn ẹgbẹ́ gbẹ́ jọdá nìkàn ló péju, àwọn ọdọ náà jáde wá láti yẹ́ àṣ]a ìbílẹ̀ sí
Àkọlé àwòrán,
Aláàfin Ọyọ, ikú bábá yèyé, Ọba Lamidi Adeyemi náà péjú síbi ayẹyẹ ojúde Oba ní'lú Ijebu
Àkọlé àwòrán,
Gómínà ìpínlẹ̀ Ogun, Dapo Abiodun àti Awùjalẹ̀ Ijẹ̀bú Ọba Sikiru Adetona
Àkọlé àwòrán,
Gómìnà tẹ́lẹ̀rí ní ìpínlẹ̀ Ogun, Ọtunba Gbẹnga Daniels
Àkọlé àwòrán,
Ẹgbẹ́ Bọ́baguntẹ ilẹ̀ Ijẹbu
Àkọlé àwòrán,
Gbogbo ojú tó ti ríra típẹ tún ni àànfàni láti ṣe "Ẹ k;u àti"
Àkọlé àwòrán,
Ẹgbẹ́ Obafunwaji Obinrin Adedoyin rèé nínú aṣọ ofi aláwọ̀ búlù
Àkọlé àwòrán,
Ẹgbẹ́ Tobalaṣẹ Ọkunrin náà ko gbẹ́yìn
Àkọlé àwòrán,
Gbogbo àwọn ọmọ ẹgbẹ́ Gbobaniyi lókùnrin àti lóbìrin ló ti lọ ki ọba aláde lóri ìjòkò
Fo Móríwú kọjá kí o tẹ̀síwájú
Móríwú
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ
05:33
Fídíò,
Tírélà ló pa ọkọ mi tó jẹ́ awakọ̀ èrò, ìdá mẹ́ta ẹ̀bùn owó ló kàn mì, ìyá ọkọ mi kò bèèrè àwọn ọmọ di ìsinyìí - Opó
, Duration5,33
02:29
Fídíò,
Irọ́ ni Portable n pa wí pé mo gé òun jẹ, ohun tó ṣẹlẹ̀ lásìkò ìjà wa rèé - Charles Okocha
, Duration2,29
02:46
Fídíò,
Wo pàtàkì òrìṣà Vodu Dangbe, níbi táwọn olùjọ́sìn ti ń gbé ejò sọ́rùn, kẹ̀yìn sí ìbálòpọ̀, jíjẹ epo tàbí iyọ̀ ṣaájú ètùtù
, Duration2,46
05:13
Fídíò,
Òṣìṣẹ́ báǹkì tó di ẹni tó ń ta pọ̀nmọ́ aláta lọ́jà nílùú Ibadan
, Duration5,13
03:37
Fídíò,
Ǹjẹ́ ó tọ́ kí òbí máa kàn án ní dandan f'áwọn ọmọ láti tọ́jú wọn lọ́jọ́ ogbó?
, Duration3,37
05:53
Fídíò,
Ìtàn Balogun Oderinlo tí àjà gbé lọ fún àádọ́rin ọjọ́, ó padà dé pẹ̀lú àpò àbìrà tí ọ̀sanyìn wà, ó di alágbára fún Ibadan
, Duration5,53
02:30
Fídíò,
Wo ọ̀pọ̀ àǹfààní ẹyẹ Igún àti ewu tó wà nínú bí ẹyẹ náà ṣe ń tán lọ nílẹ̀ wa
, Duration2,30
02:54
Fídíò,
Ṣé lóòtọ́ọ́ ni àwọn ẹ̀gbọ́n Ademola Adeleke ti já àkóso ìjọba Osun gbà mọ́ ọ lọ́wọ́? Àlàyé rèé
, Duration2,54
05:26
Fídíò,
Àwọn dókítà ti sọ fún mi pé kí n dẹ́kun sígà fífà àti ọtí mímu-Tope Osoba. Nibo Laye Koju Si?
, Duration5,26
02:30
Fídíò,
Nǹkan kan tí mo mọ̀ ni pé bí orin tí mo bá kọ bá bùkún fún mi, yóò bùkún fún gbogbo èèyàn tó bá gbọ́ ọ - Bisi Manuel
, Duration2,30
03:24
Fídíò,
Àwọn olólùfẹ́ Kola Oyewo sọ̀rọ̀ nípa rẹ̀ lẹ́yìn ìsìnkú rẹ̀
, Duration3,24
04:02
Fídíò,
Àwọn sinimá kan wà tí mo ṣe tí àwọn òbí mi kò lè wò nítorí… - Bolaji Ogunmola, òṣèré tíátà
, Duration4,02
Ìparí Móríwú
Ìròyìn tó ṣe kókó
Gani Fawehinmi: Agbẹjọ́rò àti ajàfẹ́tọ̀ọ́ ọmọniyàn ni Nàìjíríà ti ọ̀rọ̀ tálákà jẹ lógún
ìṣẹ́jú 20 sẹ́yìn
Ṣé òótọ́ ni pé INEC ti mọ ẹni tí yóò jáwé olúborí kí ètò ìdìbò tó wáyé?
wákàtí 4 sẹ́yìn
Ìjọba Plateau gbé gbogbo ilé ẹ̀kọ́ tì pa nítorí àrùn Diphtheria tó búrẹ́kẹ níbẹ̀
wákàtí kan sẹ́yìn
Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn
A ti gba mílíọ́nù márùndínlọ́gbọ̀n Náírà owó tí Ogogo gbé fún Ìmáàmù àgbà Ilaro padà - Ẹbí Ogogo
1 Owewe 2026
Ṣé lóòótọ́ ni OPay fẹ́ kógbá wọlé ní Naijiria lónìí ọjọ́ kíní oṣù Kẹ́sàn án? Ohun tí a mọ̀ rèé
1 Owewe 2026
Àlàyé rèé lórí ipa táwọn ikọ̀ aláàbò kó lórí báwọn Àgùnbánirọ̀ mẹ́ẹ̀dógún, aráàlú mẹ́fa, tí wọn jí gbé ní Kogi, ṣe gba ìtúsílẹ̀ àti ohun tí ààrẹ Tinubu sọ
1 Owewe 2026
Lẹ́yìn ọgbọ̀n ọdún, ilé ẹjọ́ kéde olórí ikọ̀ gàńfé bí ẹni tó jẹ̀bi ẹ̀sùn ikú Tupac Shakur
1 Owewe 2026
Àlàyé rèé lórí ohun táwọn dókìtà nílé ìwòsàn LAUTECH ń bèèrè fún, bí ìyanṣẹ́lódì wọn ṣe wọ ọjọ́ mẹ́rin
31 Ògún 2026
A ti ṣetán láti ṣàtìlẹ́yìn fún ìjọba lórí ètò ààbò tó mẹ́hẹ – OPC
30 Ògún 2026
Wo àwọn ọ̀nà tí o lè gbà láti ṣọ́ owó ná lórí oúnjẹ lásìkò ọ̀wọ́ngógó yìí
30 Ògún 2026
Gómìnà Adeleke, mo kí ẹ kú oríire pé o wọlé fún sáà kejì àmọ́ ọ̀rọ̀ sì kù lẹ́yìn rẹ̀ - Oyebamiji, olùdíje gómìnà APC l'Osun
30 Ògún 2026
Wo ìdí pàtàkí mẹ́rin tí Ààrẹ Tinubu kò ṣe fẹ́ kí ilẹ̀ Amẹ́ríkà fí àkọsílẹ̀ rẹ̀ nípà egbòogi olóró síta
30 Ògún 2026
Ìròyìn tí àwọn ènìyàn fẹ́ràn jùlọ
1
Ìjọba Eko fèsì sí ẹ̀sùn tí obìnrin kan fi kan ilé ìwòsàn Randle nínú fídíò tó gba orí ayélujára
2
NRC àti NSCDC dá ìgbìyànjú fífọ́ àti jíjí ohun èlò ojú irin dúró l'Osun
3
Àṣírí gbọ́mọgbọ́mọ méjì tó ń wọ Hijab láì ṣe Mùsùlùmí tú lásìkò tí wọn tún fẹ́ jí ọmọ míì gbé
4
Sunday Igboho sọ̀rọ̀, orí ayélujára tún gbóná jain-jain, áláyé rèé
5
A ti gba mílíọ́nù márùndínlọ́gbọ̀n Náírà owó tí Ogogo gbé fún Ìmáàmù àgbà Ilaro padà - Ẹbí Ogogo
6
Wo ipa tí mímú àlékún bá iye owó lílẹ pátákó ìpolongo ìbò máa ní lórí ètò ìdìbò 2027
7
Àlàyé rèé lórí bí a ṣe ṣàwárí, dóòlà àwọn tí ajínigbé gbé ní Oriire, ọ̀nà táwọn èèyàn mẹ́sàn-án gbà kú àti ọ̀pọ̀ òfegè ìròyìn nípa ìṣẹ̀lẹ̀ náà - Ọ̀gá DSS
8
Ìjọba Plateau gbé gbogbo ilé ẹ̀kọ́ tì pa nítorí àrùn Diphtheria tó búrẹ́kẹ níbẹ̀
9
Àṣírí ibi tí wọ́n ti n ṣe ayédèrú owó Euro tú n'ibadan, àwọn afurasí há
10
Báyìí ni ìgbẹ́jọ́ awakọ̀ Anthony Joshua tún ṣe lọ àti àwọn kókó ẹ̀sùn mẹ́rin tí olùpẹ́jọ́ gbé kalẹ̀
You might also like:
news
|
sport
|
weather
|
worklife
|
travel
|
future
|
culture
|
world
|
business
|
technology