BBC News,
Yorùbá
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀
Ìròyìn
Wò
Gbọ́
Àwọn abala
Ìròyìn
Eré ìdárayá
Èyí to gbajúmọ̀ jù
Eré ìdárayá
Èyí to gbajúmọ̀ jù
Coronavirus: Báyìí ni nkan ṣe n lọ ní pápákọ̀ ọkọ̀ òfurufú l'Eko lẹ́yìn tí Coronavirus wọ́lé
Àkọlé àwòrán,
Gbogbo awọn to n wọle, tabi jade kuro ni papakọ ofurufu Murtala Muhammed lo n gba abẹ ayẹwo kọja
29 Èrèlè 2020
Àkọlé àwòrán,
Yatọ si irinṣẹ ti wọn n mu dani, ẹrọ kan tun wa bi kamẹra to n ṣe ayẹwo awọn eero baalu fun apẹẹrẹ aarun Coronavirus
Àkọlé àwòrán,
Oriṣiriṣi awọn oṣiṣẹ eto ilera lo wa ni ikalẹ ni papakọ ofurufu ilu Eko fun ayẹwo awọn arinrinajo
Àkọlé àwòrán,
Koda, wọn gbe omi aporo kokoro aifojuri 'sanitizer' silẹ fun awọn arinrinajo
Àkọlé àwòrán,
Ati oṣiṣẹ ati eero baalu lo n lo iboju lati ba ara wọn sọrọ nitori Coronavirus
Àkọlé àwòrán,
Kii ṣe ita papakọ ofurufu nikan ni ikiyesara ti n waye, gbagbaagba ni kaluku n boju-bomu ninu ọfiisi.
Àkọlé àwòrán,
Ẹrọ ayaworan wa tun gbe oṣiṣẹ eto ilera kan to wa lẹnu iṣẹ t'oun ti iboju ati ìbọ̀wọ́
Àkọlé àwòrán,
Ṣugbọn o, Coronavirus ko da wiwọle ati jijade ni Naijiria duro ni papakọ ofurufu naa. Kẹti-kẹti ni eero n ya lati wọ baalu.
Àkọlé àwòrán,
Igbesẹ oju lalakan fi n sọri ọhun ko yọ awọn oṣiṣẹ ajọ to n risi iwọle-wọde (Immigration) silẹ. Iboju lawọn naa fi ṣe koju o ma ri ibi.
Móríwú
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ
03:51
Fídíò,
Wọ́n kó Rasheed mérò níbi ìwọ́de EndSARS lọ́dún 2020, ọdún mẹ́fà ló lò lẹ́wọ̀n
, Duration3,51
02:00
Fídíò,
Àkọsílẹ̀ DNA ṣàwárí àwọn ọmọ tí bàbá wọn ti sọnù fún ọ̀pọ̀ ọdún
, Duration2,00
05:19
Fídíò,
Timini ṣàlàyé fún BBC lórí ohun tó ṣẹlẹ̀ láàrin òun àti Funke Akindele
, Duration5,19
04:19
Fídíò,
Bàbá àti ọmọ ni Olubadan àti Makinde, kò yẹ kí ìjà máa wáyé láàárín wọn - Balogun Olubadan
, Duration4,19
03:37
Fídíò,
N kò ní darapọ̀ mọ́ ẹgbẹ́ ADC àmọ́ bí APC bá fún mi ní ipò míì, màá gbà á - Iyabo Obasanjo
, Duration3,37
02:44
Fídíò,
Ilẹ̀ Cameroun fi tijó-tìlù pàdé Pope Leo XIV
, Duration2,44
02:33
Fídíò,
Ẹni tó bá ní kò sí ayé, ayé wà o, ohun tó jẹ mọ́ ọ̀rọ̀ ẹ̀mí wà nínú iṣẹ́ tíátà - Tosin Olaniyan
, Duration2,33
01:25
Fídíò,
Kí ló sọ àwọn ológbò di gbajúmọ̀ orí ayélujára ní Instabul?
, Duration1,25
03:16
Fídíò,
Kí ni ẹ̀ṣẹ̀ wa ní Ido-Ani, tí ìjọba Ondo fi pa wá tì láìsí ilé ìwòsàn àti ojú ọ̀nà tó dára? – Aráàlú fárígá
, Duration3,16
04:12
Fídíò,
Àwọn òṣèré òde òní nílò láti máa ṣàgbéyẹ̀wò ìtàn tí wọ́n ń kọ, a kìí ṣe eégún oníhòhò - Lere Paimo
, Duration4,12
06:34
Fídíò,
Ọba Ido-Osun pàṣe kí wọ́n ti ilé ìjọsìn tí pásítọ̀ rẹ̀ lọ gbàdúrà lójúbọ Osun Osogbo pa
, Duration6,34
05:05
Fídíò,
Kí ni ohun abàmì tó wà nínú Omi Oko ní Ilesa, tí wọn ṣe kọ́lé fún-un, yọ fèrèsé àti ìlẹ̀kùn sí?
, Duration5,05
Ìròyìn tó ṣe kókó
Awodi: Òrìṣà òjò tí abọrẹ̀ rẹ̀ kò gbọdọ̀ ru ẹrù tàbí ṣe aṣemáṣe pẹ̀lú obìnrin
wákàtí kan sẹ́yìn
Wo nǹkan mẹ́tàdínlógún tí ìjọba ti fòfin dè pé wọn ò gbọdọ̀ kò wọlé sí Naijiria mọ́ látòkè òkun
ìṣẹ́jú 13 sẹ́yìn
APC kéde ₦100m bíi owó fọ́ọ̀mù ìdíje ipò ààrẹ, làwọn ọmọ Nàìjíríà bá pariwo
ìṣẹ́jú 55 sẹ́yìn
Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn
A gbàgbọ́ pé àlàáfíà yóò jọba ní Cameroon lẹ́yìn àbẹ̀wò Pope Leo XIV- Aráàlú
15 Ìgbé 2026
Kí ni Cute Abiola ṣe, tí omíjé fi ń dà lójú rẹ̀ àmọ́ tí ọ̀pọ̀ èèyàn ń sọ̀rọ̀ si?
16 Ìgbé 2026
Àlàyé rèé lórí ìdí tí ìjọba ṣe yọ ẹ̀sùn fifi owó ṣèrànwọ́ fún ìgbẹ́sùnmọ̀mí kúrò nínú ẹjọ́ ti Malami ń jẹ́
16 Ìgbé 2026
Ogun Abẹ́lé Sudan: Akọ̀ròyìn tó há sínú ogun fún ọdún mẹ́ta sọ ohun tójú rẹ̀ rí
16 Ìgbé 2026
Ibà ọ̀rẹ̀rẹ̀ (Lassa Fever) wọ ìpínlẹ̀ Oyo, wo ọ̀nà márùn-ún láti dènà rẹ̀
16 Ìgbé 2026
Ipa wo ni àìsí aṣojú INEC níbi ìpàdé àpérò ADC yóò ní lórí ẹgbẹ́ òṣèlú náà?
16 Ìgbé 2026
Ìgbà ìkẹyìn tí máà díje fún ipò ààrẹ rèé, tí ń kò bá borí ìbò abẹ́nú, máa ṣe àtìlẹyìn fún ẹni tí ADC bá fà kalẹ̀ láti díje ipò ààrẹ - Atiku
16 Ìgbé 2026
Ọwọ́ ọlọ́pàá tẹ afurasí mẹ́fà tó fẹ́ ju àdó olóró sí dúkìá ìjọba l'Ondo
16 Ìgbé 2026
"Ẹ̀yin ọ̀dọ́ tí ẹ̀ ń kún pé bí Toun Soetan ṣe ń kọrin ń di yín lọ́wọ́ láti dárà nínú ìjọ, ó ti lọ, ẹ wá dárà yín ká rí i"
17 Ìgbé 2026
Ìròyìn tí àwọn ènìyàn fẹ́ràn jùlọ
1
Níṣojú mi báyìí ni wọ́n ṣe ṣá ọkọ mi ládàá pa ṣùgbọ́n mi ò lè pariwo kí wọ́n má bàá ṣá èmi náà-Ìyàwó olóyè Ibadan
2
Bàbá kan yìnbọn pa ọmọ rẹ̀ méje àti ọmọ ọlọ́mọ kan
3
Irọ́ ni pé a ti dá ẹ̀yáwó tí à ń ṣe fún àwọn akẹ́kọ̀ọ́ dúró - NELFUND
4
A ti yanjú aáwọ̀ láàárín Makinde àti Olubadan-Ìgbìmọ̀ ọmọ Ibadan
5
Àwọn ọlọ́pàá tó ti fẹ̀yìn tì lẹ́nu iṣẹ́ ṣèwọ́de l'Abuja lórí owó ìfẹ̀yìntì sísan, gbégi dínà ilé-iṣẹ́ Ààrẹ
6
Ìdí rèé tí a fi ń ra màálù kan ní ₦2.5m báyìí, àwọn alápatà sàlàyé
7
Wíwẹ̀ ní àárọ̀ tàbí alẹ́: Èwo ló dára jùlọ?
8
Ọba kì í ṣe òṣèlú, Olubadan, ẹ jáwọ́ níbẹ̀ kẹ́ ẹ má baà mú àrífín wá - Balogun Olubadan
9
Àlàyé rèé lórí ìdí tí ìjọba ṣe yọ ẹ̀sùn fifi owó ṣèrànwọ́ fún ìgbẹ́sùnmọ̀mí kúrò nínú ẹjọ́ ti Malami ń jẹ́
10
APC kéde ₦100m bíi owó fọ́ọ̀mù ìdíje ipò ààrẹ, làwọn ọmọ Nàìjíríà bá pariwo
You might also like:
news
|
sport
|
weather
|
worklife
|
travel
|
future
|
culture
|
world
|
business
|
technology